The Book of Revelations 11: 19, 12: -1, 6
11:19 | A si ṣí tẹmpili Ọlọrun silẹ li ọrun. A sì rí àpótí Májẹ̀mú rẹ̀ nínú tẹ́ńpìlì rẹ̀. Ati mànamána ati ohùn ati ãra si wà, ati ìṣẹlẹ, ati yinyin nla. |
12:1 | Àmi ńlá sì hàn ní ọ̀run: obinrin ti a fi õrùn wọ, oṣupa si mbẹ labẹ ẹsẹ rẹ̀, adé ìràwọ̀ méjìlá sì wà ní orí rẹ̀. |
12:6 | Obìnrin náà sì sá lọ sí àdáwà, níbi tí a ti múra àyè sílẹ̀ láti ọ̀dọ̀ Ọlọ́run, ki nwọn ki o le ma bọ́ rẹ̀ ni ibẹ̀ fun ẹgbẹrun ọjọ o le ọgọta. |
Leave a Reply
You must be logged in to post a comment.